Posts

Showing posts from December, 2017

ÌJỌBA TÍ KÒ SÍ LỌ́WỌ́ ÀWỌN ỌBA NI KÒ JẸ́ KÍ AYÉ Ó GÚN RÉGÉ MỌ́ – OLUWO

Image
Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdul-Rasheed Adewale ni ohun ti ko je ki aye roju mo ko jina lati wa kiri. O ni ijoba ti ko si lowo awon Oba mo lo faa. O ni Oba nikan lo n ba Eledumare je oruko po ti awon wa je eni to wa laarin awon ara ilu ati Eledua. O ni awon ni Eledua fi gbogbo akoso ile aye le lowo, nitori pe Oba ni oko oso, oko aje ati oko elebo-loogun. Ti eku ko ba ke bi eku mo, ti eye ko ke bi eye mo tabi omo eniyan ti ko fohun bi omo eniyan. Oba nikan lo mo ohun ti a n se. Oba nikan lo mo bi a se n be awon alale ti gbogbo nnkan si maa bere si ni tuba-tuse. Oluwo pe akiyesi si asiko ti o je pe Oba lo n dari gbogbo nnkan ni ilu, o ni eyi to ba fe ru won loju, won mo bi won se n fi ese ile too, sugbon ti ko ri bee mo ni aye ode oni. Oluwo ni peluu bi o se ri yii naa, a ko gbodo kawo gbera, a ni lati kun won lowo naa ni nitori pe “Aafaa to ni iyan yoo mu, omo tire naa ko ni je tira”.

MO MAA N SA FUN AWON OBINRIN TO BA FE BA MI SE ISEKUSE – AKIN LEWIS

Image
Agba osere Akin Lewis, ti so pe opo obinrin lo maa n konu si oun pe ki won jo ni ibalopo. O ni ti o ba je pe gbogbo obinrin to ti konu si oun pe ki won jo ni asepo ni oun ba gba fun ni, boya un kiba ti ku bayii. O so fun awon oniroyin pe oun ti oun maa n se nip e oun maa n sa danu ti obinrin kan ba ti denu ibasun ko oun. O ni iyawo oun ni olubadamoron ati ore timotimo oun, to si je pe un kii maa be sita mo bi oun se maa n se tele.

OSUPA ATI PASUMA GBE IJA WONU ODUN TUNTUN

Image
Adura alaafia ati irepo ti awon eniyan kan gba fun agbo fuji gba die, sugbon adura naa ko gba tan o. Ni odun to n pari yii, ija to wa laarin awon ogbologbo onifuji meji, Saheed Osupa ati Wasiu labi Pasuma, tun je jade. Koda, ija naa ko pari rara. Ija naa jeyo ni nnkan bii ose meji seyin, nigba ti ayeye ojo ibi alaadota odun Pasuma waye. Opo osere lo lo ba Pasuma se ajoyo, ti won si sere funun.  Lara won ni King Sunny de ati Wasiu yinde K1 de Ultimate. Sugbon Osupa ati Malaika ko lo sibe. Eyi tumo sip e won ti gbe ija naa wo inu odun tuntun.

IDI TI MO FI SO OMO MI NI FEMI ADEBAYO – OGA BELLO

Image
Osere pataki, Alagba Adebayo Salami, ti so asiri bi o se so omo bibi inu re ti oun naa je elere fiimu, Femi Adebayo, ni oruko to n je di oni olonii. O so ninu iforowanilenuwo kan pe oun so o ni Femi lati fi se ayesi fun baba-nigbejo oun kan ni, ti eni naa je Alagba Femi Okunnu. Loya pataki ni baba naa je ni Eko, to si ti se opo ejo nla-nla ni aseyori. Oga Bello ni ise loya lo wu oun lati se tele. O ni aisi owo ni ko je ki oun lo kawe gboye lori re. O ni oun sise gege bii akowe ni oofisi Alagba Femi Okunnu nigba kan, ti baba naa si je baba-igbejo, iyen godfather fun oun di oni olonii. Oga Bello wa salaye pe nigba ti oun bi Femi, ti oun fe so o loruko, oun wa pinnu pe oruko ti baba-nigbejo oun n je naa ni oun yoo fun un. Oga Bello ni ninu gbogbo fiimu ti oun ti se, ASEWO TO RE MEECCA lo gbayi ju, to fun oun lowo ju, to si tubo so oun di ilumo-o-kaa.

5TH YEAR REMEMBRANCE OF GLORIOUS EXIT OF A RARE GEM "BISI KOMOLAFE".

Image
It may look like remembrance of unbearable pain in the minds of her families, friends and fans but there is nothing we can do about it. As I, CyberProf-Alabi Samuel-Johnson NoWay ForOpposition promised all of us in this forum that I wouldn't be reluctant to keep us updated concerning past and present issues happening in the ancient city of Ibadan, Oyo State and Nigeria at large, I am hereby reminding us concerning the death of our beloved Ibadan actress who died in 2012. GLOOM enveloped Ibadan, the Oyo State capital, going to 5 years as the body of popular Yoruba actress, Bisi Komolafe, was buried. Family members, friends, admirers and other sympathizers sobbed uncontrollably as people gathered to bid farewell to the talented actress.  The mass, which held at St. Mary’s Catholic Church, Oke- Padre, Ibadan, was conducted by Rev. Father Benedict Ugwoegbu. Rev. Fr. Benedict Ugwoegbu, in his sermon said: “Death is no respecter of anybody. Everybody’s turn will come; do not

“MY HEART IS FILLED WITH SADNESS” – PASUMA WONDER CONDOLES WASIU AYINDE OVER DAUGHTER'S DEATH

Image
Fuji Singer, Alabi Pasuma a.k.a Pasuma Wonder has reached out to King Wasiu Ayinde a.k.a Kwam 1 over his daughter’s death, in the early hours of Tuesday, in Canada from diabetic complications. According to Pasuma Wonder, 34-year-old Wasilat Anifowese’s death has filled his heart with sadness. Pasuma said that “speechless @kingwasiuayindemarshal, Words cannot express how deeply sorry I am to hear about Wasilat, My deepest sympathy for your loss. My thoughts and prayers are with you and your entire family.  May your beautiful memories sustain and bring comfort to you during this difficult season. My heart is filled with sadness. Please accept our deepest sympathies and know that my prayers are with you during this time Sir.”

INÚ ẸGBẸ́ ÒSÈLÚ APC NÁÀ NI MO SÌ WÀ – SARAKI

Image
Aare ile igbimo asofin agba, Omowe Bukola Saraki ati olori ile igbimo asoju, Alagba Dogara pelu awon oloselu to loruko ninu egbe oselu APC ni won lo sabewo si Alagba Uche Secondus to jawe olubori gege bi alaga gbo-gbo-gbo fun egbe oselu PDP. Abewo yii wa je ki awon kan maa gbee kiri pe Saraki ati awon kan to loruko ninu egbe oselu APC fe pada sinu egbe oselu PDP. Saraki ni ko si ohun to joo lowo bayii. O ni bi ilu se maa toro, ti awon ti ko n’ise maa r’ise, ti owon gogo gbogbo nnkan maa wale ni o koko je oun logun bayii, kii se kikuro ninu egbe kan bo si omiran.

WIFE OF PRESIDENT, AISHA BUHARI SPOTTED IN “KEKE NAPEP

Image
A photo of Aisha, wife of President Muhammadu Buhari, inside the tricycle better known as ‘Keke NAPEP’, is trending on social media. She sat comfortably in the passengers’ corner and posed for photographs. It’s not clear when the picture was taken but there are unconfirmed reports that it was during her visit to Katsina to inaugurate children and maternity clinic at the General Hospital, Daura, hometown of her husband

WASIU AYINDE CRIES OVER HIS DEAD DAUGHTER

Image
Popular fuji musician, Alhaji Wasiu Ayinde , has paid tribute to her daughter , Wasilat Olaronke Ashabi Ayinde , who passed on in Canada on Tuesday. Wasilat was said to have died after an undisclosed illness . Many people have since been expressing condolences to the musician otherwise called K 1 de Ultimate over the incident . Ayinde , however, broke his silence on Thursday in a tribute he wrote to the daughter , describing her as a gift from God . The musician wrote, “ My Olaronke Ashabi: 17 th, July , 1983 to 12 th , December 2017. These are two dates in history that shall never be forgotten ever in my life . The first , a date you came to this world , and the latter , the day you departed. I give glory and thanks to God Almighty who gave you to me for a purpose . I have seen that several times , that I am privileged to have been your father and also for you to the kind of a child that also doubled as my friend . “ About your sickness, all our efforts, through med

CELEBRITIES STORM FUJI MUSIC STAR, MALAIKA 200 MILLION NAIRA LEKKI HOUSE

Image
Fuji music star, Alhaji Sulaimon Alao Adekunle popularly known as Malaika is enjoying the euphoria of his 200 million naira Lekki house warming ceremony that took place on Sunday 10th December 2017 at Salvation Avenue, Kajola, Ibeju Lekki, Lagos. King of Fuji music, Alhaji Wasiu Ayinde ‘K1’, Alhaji Saheed Osupa, Alhaji Abass Akande Obesere, Alhaji Sefiu Alao, Alhaji Kollinton Ayinla with other colleagues were role calls. Islamic Scholars that attended the event were Sheik Muyindeen Ajani Bello, Sheik Surajudeen Asuquna, Sheik Yusuf Abolore Okutadidi . And Islamic singers were Alhaja Rukayat Gawat, Alhaji Sauti Arewa and Alhaja Kafayat Singer, Alhaja Mistura Success. Global Excellence publisher, Mayor Akinpelu, and City People publisher, Seye Kehinde, Kunle Raheed, Charles Nwagbara, Tade Asifat also attended the memorable event with other well-wishers.

KWAM 1 SPEAKS ON DAUGHTER'S DEATH

Image
The popular Fuji musician, Wasiu Ayinde Marshal, also known as Kwam 1, has confirmed the death of one of his daughters, Wasilat. Wasilat died in Canada after a brief illness. The deceased, said to be 34 years old, reportedly died in the early hours of Tuesday from complications arising from diabetes. On Thursday, Kwam 1 extolled the virtues of his late daughter while saying he accepts her death as the will of Allah. He wrote: “17th July 1983 -12th December 2017, The two dates in history and shall never be forgotten ever in my life. The first, a date you came to this world and the later the day you departed. “I give glory & thanks to God Almighty who gave you to me as a gift by you coming to this world for a purpose and through me. I have seen that severally while you were growing that I am privileged to be your father and also to the kind of a child that also double as my friend. “About your sickness and all our efforts through medical means that was availabl

ỌYỌ STATE INAUGURATES 14-MEMBER PRIMARY HEALTHCARE BOARD

Image
Oyo State governor, Senator Abiola Ajimobi, has charged members of the Oyo State Primary Health Care Board to ensure an efficient and effective healthcare delivery at the state’s primary healthcare centres and health posts. Governor Ajimobi, represented at the inauguration of the board by the state’s Commissioner for health, Dr Azeez Adeduntan, said this would ensure that general hospitals are decongested and work optimally. The governor said that governments all over the world invest in primary healthcare centres to boost access to healthcare, especially for indigent persons, urging them to put in their best to make the agency thrive. Acting Executive Secretary, Oyo State Primary Health Care Board, Dr Lanre Abass, in his presentation on the agency’s journey so far, said the board, among other things, would be expected to help determine the minimum resources required for health clinics, health posts and primary healthcare centres in the state. Noting that Oyo State has 686

AJIMOBI PRESENTS N267bn 'BUDGET OF STABILISATION'

Image
Oyo State Governor Abiola Ajimobi has presented a budget of N267billion to the State House of Assembly for ratification and approval. The presentation of the proposal tagged 'Budget of Stabilisation',  The 2018 budget is N60billion greater than the 2017 budget of N207billion and N94billion higher than the 2016 budget of N173billion. In essence, the government is expecting about N93billion from the Federation Account in 2018 compared to N69billion that was received in 2017. The internally generated revenue for the coming year is projected at N112billion compared to 2017 projection of N107billion, as the increase in revenue is based on cost-effective revenue collection through the passage of relevant laws. Total recurrent is also projected at N213billion while the capital receipts are estimated at N43billion compared to 2017 estimates of N183billion as recurrent and N24billion as capital receipts for 2017. A breakdown of the 2018 budget revealed that recurrent e

OLUBADAN: MOGAJIS ISSUE SEVEN-DAY ULTIMATUM TO 21 IBADAN KINGS

Image
The Ibadan M ogajis (family heads) , under the aegis of Council of Authentic Ibadan Mogajis, have issued a seven -day ultimatum to the 21 kings installed by the Oyo State Governor, Abiola Ajimobi, to withdraw their threat to recommend Olubadan of Ibadan land, Oba Saliu Adetunji , for removal or face the wrath of Ibadan people . The 21 kings , who were on August 27 , 2017 installed by the governor , had on Monday given a 21 -day ultimatum to the monarch to be of good conduct or risk being removed from the throne. At a press conference addressed by the 21 kings at Mapo Hall , Ibadan, the Oyo State capital , leader of the group, Oba Lekan Balogun , who is also the Otun Olubadan of Ibadan land, accused the monarch of taking unilateral decisions on behalf of the ‘Olubadan-Kings-in-Council ’ and inciting the people against the state government. At the end of a meeting held by the Ibadan Mogajis on Thursday , eight of the 21 kings , who are high chiefs in Ibadan , were urged to st